\v 20 Jésù sí dáhùn ó sì wí fún wọn pé, "Ọ̀kan nínú àwọn méjìlá, tí ó ń tọwọ́ bọ̀ inú àwo pẹ̀lu mi. \v 21 Nítòótọ́ Ọmọ ènìyàn yíò lọ bí a ti kọ̀wé nípa tirẹ̀. Ṣùgbọ́n ègbé ni fún ọkùnrin nâ tí yíò jé sábàbí ìdàlè Ọmọ ènìyàn! ìbá sàn fún ọkùnrin náà tí a kò bá bí sáyé rárá.